Ilé-iṣẹ́ ọmọ-ogun Òfurufú tí Nàìjíríà, NAF, ní wọ́n tí gbóríyìn fún látári àwọn ìgbésẹ̀ lórí àwọn apànìyàn jayé pẹ̀lú àwọn ọkọ Òfurufú tí á kó fún wọ́n.
Mínísítà tí Ààbò, Mohammed Badaru tó ṣé ìwúrí náà láti ẹnú agbẹnusọ tí ilé-iṣẹ́ Ìjọba, Henshaw Ogubike sọ pé, ṣiṣé àfihàn pàtàkì àwọn ọkọ̀ ìjà Òfurufú fún ààbò tí orílẹ̀-èdè.
Ayẹyẹ náà ṣé àfihàn ìpinnu Nàìjíríà lórí ìmúdójúìwọ̀n àwọn ọmọ-ogún rẹ̀.