Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Tẹlé Ri Fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Buhari Kí Babangida Kú Ayẹyẹ Ọjọ́ Ibí Ọdún Méjìlélọ́gọ́rin.

0 205

Ààrẹ àná fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari, tí fi ayọ rẹ hàn lórí ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Ọdún Méjìlélọ́gọ́rin tí Ààrẹ Ológun tẹ́lẹ̀ rí fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ọ̀gagun Babangida pé lórí ilẹ alààyè.

Nínú atẹjade kan láti ọwọ́ agbẹnusọ rẹ , Ààrẹ tẹ́lẹ̀ rí ṣe àpèjúwe Babangida gẹ́gẹ́ bí Akinkanju Okunrin ti Óruko rẹ ko le parẹ nínú ìwé àwọn akọni.

Ó ni nínú ìwé ìtàn Orílẹ̀-èdè pẹ̀lú, Oruko Babangida ko le parẹ láíláí.

Ó wa ki Babangida àti ádùrá wí pé Ọlọrun a túbọ̀ lọ́ra Èmi rẹ pẹ̀lú àlàáfíà tó pé yé.

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button