Take a fresh look at your lifestyle.

Adarí Nàìjíríà yóò dúró ọ̀ṣẹ̀ kan si ní London

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

0 214

Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò dúró ọ̀sẹ̀ kan síi ní London, United Kingdom,bí Dókítà eyín rẹ̀ ṣe sọ,tí ó sì ti ń ṣètọ́jú rẹ̀.

Dókítà ní láti ṣètọ́jú ààrẹ fún ọjọ́ márùn ún mìíràn tí ó sì ti bẹ̀rẹ̀ báyìí.

Ààrẹ Buhari darapọ̀ mọ́ àwọn adarí tókù lágbàáyé láti kópa nínú ìwúyè Ọba Charles kẹta,ní ọjọ́ kẹfà,oṣù Ebìbì, 2023.

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button