Ààrẹ Bola Tinubu tí fọwọ́sí Àtúnṣe Òfin Ìlànà Ìdìbò 2026, ọjọ́ díẹ̀ lẹ́yìn tí Àjọ Olómìnira Elétò Ìdìbò tí Orílẹ̀-èdè (INEC) ṣàfihàn àkókò àti ìlànà ìdìbò gbogbogbòò fún ọdún 2027.
Ayẹyẹ ibuwọlu náà wáyé ní Ilé-iṣẹ́ Ààrẹ, Abuja, ní nkán bíi aago márùn ún (5:00 pm) irọlẹ ní Ọjọ́rú, pẹ̀lú àwọn olórí aṣojú ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ti Orílẹ̀-èdè yìí lẹyin ti àwọn aṣòfin náà tí buwọ́lù ìwé àṣẹ náà ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun.
Àtúnṣe ránpẹ́ tó wáyé lẹ́yìn ariwo àwọn aráàlú lórí àtúnṣe sí ìlànà gbígbé èsì ìbò jáde lẹsẹkẹsẹ tí wọ́n bá tí dibo tán.
Comments are closed.