Àjọ Àgbáyé fún Ìlera (World Health Organization WHO) tí kéde yíyan tí Ọ̀jọ̀gbọ́n Mohamed Janabi gẹ́gẹ́bí Olùdarí túntún fún Ẹkùn Áfíríkà tí WHO.
Yíyan náà ni a ṣé l’àkókò àpéjọ pàtàkì kán tí Ìgbimọ Àgbègbè WHO fún Áfíríkà, tó wáyé ní Geneva ní ọjọ́ Àìkú níwájú Àpéjọ Ìlera Àgbáyé.

Àpéjọ náà ní atẹle ikú òjìji tí Olùdarí Àgbègbè náà tẹlẹ, Dókítà Faustine Ndugulile, ní Oṣù kọkànlá ọdún ní 2024.
“Awọn oludije mìíràn fún ipò náà ní Dr. N’da Konan Michel Yao (ti a daba nípasẹ Côte d’Ivoire), Dr Mohammed Dramé (ti a daba nípasẹ orìlẹ̀-èdè Guinea), ati Ọ̀jọ̀gbọ́n Moustafa Mijiyawa (tí Togo dabaa),” WHO sọ nínú àlàyé kán.
Ẹkun yíyan Janabi yóò wáyé níbí àpéjọ àpéjọ ọgọrùn àti mẹ́tadínlọgọ́ta 157th tí Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ tí WHO, tí yóò wáyé látí ọjọ́ kéjìdinlọ́gbọ̀n sí ọjọ́ kọkandinlọgbọn 28 si 29 Oṣù Kàrún ní Geneva, fún ìpinnu látí pàdé ní déédé.
Comments are closed.