Ààrẹ Bola Tinubu tí kí Ààrẹ Ẹgbẹ́ Dangote, Alhaji Aliko Dangote, lórí yíyàn rẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ìdókòwò aládàáni ti banki àgbáyé.
Lekan Orenuga
Ààrẹ Bola Tinubu tí kí Ààrẹ Ẹgbẹ́ Dangote, Alhaji Aliko Dangote, lórí yíyàn rẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ìdókòwò aládàáni ti banki àgbáyé.
Ilé-iṣẹ́ Ìdókòwò Aládàáni tí Bánkì Àgbáyé jẹ́ ‘apá kán tó níí ṣé pẹ̀lú ìgbéga ìdókòwò àti ṣiṣẹda iṣẹ́ ní àwọn ètò-ọrọ àjé tó ní ìdàgbàsókè ‘.
Nínú àlàyé kán tí Olùdámọ̀ràn pàtàkì sí Ààrẹ lórí Àlàyé àti Ìlànà, Ọ̀gbẹ́ni Bayo Onanuga, Ààrẹ tí rọ́ Dangote látí fakọyọ pẹ̀lú àwọn ìmọ̀ràn ìyípadà káàkiri àgbáyé ni kíkún.
Bánkì Àgbáyé kéde ìpinnu láti pàdé pẹ̀lú Dangote ní Ọjọ́bọ̀ gẹ́gẹ́ bi apakan látí rí imugboroosi gbooro ti Laabu Idoko-owo Aladani rẹ.