Take a fresh look at your lifestyle.

Ìròyìn Ayọ̀: Àrùn Ebola Di Ohun Àfìsẹ́yìn Tí Egúngún Ń Fi Asọ Ní Orílẹ̀-èdè Uganda- Minisita Ètò Ìlera

140

Ènìyàn mẹ́jọ tí àyẹ̀wò fi hàn pé àrùn Ebola ń yọ lẹ́nu nígbà tí àrùn náà  súyọ ní ọ̀ṣẹ̀ tí ó kọjá ní ó ti wà ní ipò àlàáfíà, tí wọn si ti kúrò ní ilé ìwòsàn

 

Àjọ WHO gbósùbà fún ìjọba Orílẹ̀-èdè Uganda láti ara ìgbésẹ̀ kíákíá tí ó wáyé lójúnà àti dènà ìtànkálẹ̀ àìsàn náà

 

Ìjọba àti àwọn elétò ìlera ti wà ní ojú ni alákàn fi ń sọ́rí láti rí i dájú pé ogun tí ó ti ṣẹ́, kò tún gbórí mọ́

 

Comments are closed.

button