Àdelé Ọgá Àgbà Ọlọ́pàá Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ag. IGP Egbetokun Olukayode tí gbá iṣẹ́ ní Ilé-iṣẹ́ agbofinro ní Abuja, Olú-ìlú Nàìjíríà.
IGP Egbetokun ní Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu, GCFR, tí yán ní ọjọ́ kọkandinlogun 19th, Oṣù Kẹfà, ọdún 2023.
![]()
Ó gbá ipò lọwọ́ ọgá tẹlẹ rí IGP Usman Alkali Baba, ẹni tí o fẹyinti lẹyìn ọdún kárùndínlogójì 35 kó tó feyinti lẹ́nu iṣẹ́ Ọba.
Iṣipo pada náà ló wáyé láàárín àwọn méjèèjì ní Ọjọ́rú, ọjọ́ kọkanlelogun 21, oṣù kẹfà, ọdún 2023.
Leave a Reply