gbígbógun ti òògùn olóró: Nàìjíríà, Saudi Arabia ṣerawọn lóṣùṣù ọwọ̀
Ilé -iṣẹ́ tó ń ṣòfin lórí òògùn olóró ní Orílẹ̀ -èdè Nàìjíríà, NDLEA àti Olùdarí ẹka to n gbogun ti oogun oloro lorilẹ ede Saudi Arabia (GDNC), ti gbà láti tùbọ̀ fìdí àjọṣepọ̀ wọn múlẹ̀ lórí gbígbógun ti…