Gómìnà Adamawa Ṣé Ìlérí Àtìlẹ́yìn Fún Àwọn Ilé-iṣẹ́ Ìbílẹ̀
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Adamawa, Ahmadu Fintiri, tí tún fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ sí látí ṣé àtìlẹ́yìn fún àwọn ilé-iṣẹ́ ìbílẹ̀ fún pàtàkì ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ náà àti Orílẹ̀-èdè lápapò.
Gómìnà sọ èyí dí mímọ̀ l'àkókò ayẹyẹ Ọjọ́ Ọdún àpapọ̀ Nnoma-Jhar…