Àwọn ilé ìfowópamọ́,òsìsẹ́ ìjọba, ilé ìwòsan ,kọ etí ikún sí ìyansẹlódì ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC nílùú Abùjá
Bí ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NLC) Se bẹ̀rẹ̀ ìwọ́de ọlọ́jọ́ méjì wọn láti fi se ìkìlọ̀ fún ìjọba àpapọ̀.
Síbẹ̀, púpọ̀ nínú àwọn ilé ìfowópamọ́ tó wà nílùú Abùjá ló ń bá isẹ́ wọn lọ pẹrẹu láìsí ìdíwọ́.lára àwọn ilé ìfowópamọ́…