Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Tag

Nigerian Government

Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Ní Yóó Ṣé Òkùnfà Ìdàgbàsókè Ìṣòwò Orílẹ̀-èdè Yíì – Ìgbákejì Ààrẹ Nàìjíríà

Ìgbákejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Kashim Shettima, tí ṣé àfihàn ìdúróṣinṣin òún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan pàtàkì nínú ètò-ọrọ àjé tí ìṣàkóso Ààrẹ Tinubu fún ọdún 2024. Èyí jẹ́ gẹ́gẹ́ bí Ìgbìmọ̀ ètò-ọrọ àjé orílẹ̀-èdè (NEC) ṣé tí…

Ọlọ́pàá Nàìjíríà Pín Òwò Fún Ìdílé Àwọn Ọlọ́pàá Tó Pàdánù Ẹ̀mí Wọ́n Lẹ́nù Ìṣẹ́

Ọlọ́pàá Nàìjíríà sọ pé òun tí bẹ̀rẹ̀ pínpín ìwé sọwedowo fún àwọn òṣìṣẹ́ òún tó pàdánù ẹ̀mí wọ́n làkókò tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ sìn ìlú Bàbá wọ́n àti àwọn tó ní ìfárapá èyí tó sọ wọ́n dí aláàbọ̀ àrá lẹ́nù ìṣẹ́. Ọgá àgbà fún Ọlọ́pàá IGP Usman…
button