Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Tag

NFF

NPFL Bèèrè Fún Ìgbà Láàyé Ọ̀pọ̀ Àwọn Àgbábọ́ọ̀lù Rẹ̀ Nínú Ẹgbẹ́ ‘Super Eagles’

Ìgbìmọ̀ Bọ́ọ̀lù afẹsẹgba Nàìjíríà (Nigeria Premier Football League NPFL) ń pé fún ìgbà láàyè ọ̀pọ̀ àwọn àgbábọ́ọ̀lù NPFL nínú ìkọ 'Super Eagles,' ní ìgbìyànjú láti mú ìlọsíwájú bá Lìígì àtí àwọn àgbábọ́ọ̀lù. Ìgbìmọ̀ náà sọ pé lílò àwọn…

Àwọn Àgbábọ́ọ̀lù Super Eagles Bẹ̀rẹ̀ Sí Dé Sí Ibùdó Fún Ìfẹsẹ́wọ́nsẹ́ Ife Àgbáyé 2026

Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àgbábọ́ọ̀lù Super Eagles tí bẹ̀rẹ̀ sí dé ibudó ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù náà ní ìlú Uyo ṣáájú ìfẹsẹ́wọ́nsẹ́ ìdíje ife àgbáyé tí ọdún 2026 pẹ̀lú Lesotho àtí Zimbabwe, lẹsẹẹsẹ. Jose Peseiro tó jẹ́ olukọni àgbà fún ẹgbẹ́…

Okocha Àtí Mikel Bá Orílẹ̀-èdè Turkey Kẹ́dun Lórí Ìṣẹ̀lẹ̀ ìwárírì-ilẹ̀ Tó Ṣẹlẹ̀

Àwọn àgbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tẹlẹ, Austin Okocha àti Mikel Obi tí darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn látí fí ikẹdun wọ́n ránṣẹ́ sí àwọn ẹbí àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọ́n àtí àwọn tó fí ará pá nínú ìṣẹ̀lẹ̀ tó ṣẹ̀ ní Orílẹ̀-èdè Turkey láìpẹ́ yíì.…
button