“Kòsí ìbẹ̀rù lórí ilé-ìgbìmọ̀,” – Adarí ilé ìgbìmọ̀ tẹ́lẹ̀ rí
Adarí ilé ìgbìmọ̀ tẹ́lẹ̀ rí tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ kúrò, Sẹnetọ Ovie Omo-Agege, ti sọ pé kò séwu lórí ilé-ìgbìmọ̀ pẹ̀lú bí Sẹ́nétọ̀ Godswill Akpabio ṣe jẹ́ Adarí ilé ìgbìmọ̀ kẹwàá tuntun.
Ó sọ èyí nínú àlàyé…