Ìdùnnú ṣubú layọ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Flying Eagles
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà ti ́ kò ju ogún ọdún lọ Flying Eagles, ti pegedé Fún ìdíje ife ẹ̀yẹ adúláwọ̀ 2023,pẹ̀lú àmì ayò méjì sí ọ̀kan fún orílẹ̀-èdè Ivory Coast, fún ìdí èyí, ó ti kójú òsùnwọ̀n fún…