Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger ṣèdárò àwọn afaragbà Borgu
Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger, Àringbùngbùn Arewa Nàìjíríà, Mohammed Umaru Bago, ti banújẹ́ lórí ìkọlù àwọn oníjàgídíjàgan tí ó ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ yìí ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Borgu, ti ìpínlẹ̀ náà, tí ó sì ń…