Ẹ yógun jà – Aṣojú Palestine bẹbẹ
Aṣojú Palestine sí Nàìjíríà, Abdullah Muhammad Shawesh, ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí gbogbo àgbáyé àti àwọn onínú ire ènìyàn láti ri pé ogun Gaza wá sí òpin lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.
Nigba ti o n ba awọn oniroyin sọrọ ni Eko nibi iba awọn…