Ààrẹ Tinubu gbóríyìn fún Super Eagles fún àṣeyege ìpele tí ó gbẹ̀yìn
Ààrẹ Nàìjíríà, Bọla Ahmed Tinubu, ti gbóríyìn fún Super Eagles ti Nàìjíríà fún àṣeyege ìpele tí ó gbẹ̀yìn nínú ìfagagbága ife orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀, tí Ivory Coast ṣagbátẹrù rẹ̀.
Nigba ti o n fesi lori…