Browsing Category
Uncategorized
Iyaafin Soludo, Àjọ NAWIS Sowọ́pò Lórí Ìlera Àwọn Obìnrin Pẹ̀lú Eré Ìdárayá
Ìyàwó gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, iyaafin Nonye Soludo, ti ke gbajari fún ìlera pípé nipasẹ sise eré ìdárayá ati yiyan láàyò igbesi aye àlàáfíà fún aráyé. O sọ eyi nibi Ipade pẹlu àjọ Anambra Chapter of the Association of Nigeria…
Makinde Yan Ìgbìmọ̀ Alámójútó Fún Ilé Iṣẹ́ Ìdàgbàsókè Ohun Alumọni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti yan igbimọ ti yóò máa mójú tó Ìdàgbàsókè ohun alumọni ilẹ (Pacesetter Mineral Development Company).
Gómìnà ló kéde àwọn ènìyàn mẹrin wọnyii: Ademola Ajibola, Muideen Olawale Arẹmu, Arabinrin…
Ẹ́mbáásì Amẹ́ríkà Kìlọ̀ Ìkọ̀lù Òjìjì Ní Moscow
Ẹ́mbáásì Amẹ́ríkà ni Russia ti ṣe ìkìlọ pé awon esinoòkọkú lérò ìkọ̀lù Òjìji sí ìlu Moscow ni kete ti Russia ti sọ èròngbà ibọn yíyin sí synagogue láti ọwó àwọn adìhámọ́ra ogun lati ọdọ Afghan ti Islamic State di otubantẹ́.…
Àyájọ́ Èdè Abínibí Àgbáyé 2024: Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè Èkó ṣàfihàn àṣà Yorùbá.
Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá, Ẹ̀ka Ìpínlẹ̀ Èkó ṣàfihàn èdè Ìjìnlẹ̀, ìṣe àti àṣà Yorùbá lọ́lọ́kan-jọ̀kan nínú Ayẹyẹ Àyájọ́ Èdè Abínibí Àgbáyé ọdún 2024, tí wọ́n ṣe ní gbọ̀ngàn Ilé-ẹ̀kọ́ Girama Ikeja tó wà ní ìlú Oṣòdì.
Àkórí Àyájọ́ Èdè…
Ẹ̀pa Ò Gbóró Fún Orílẹ̀-èdè Cameroon, Bí Orílẹ̀-èdè Nàíjíríà Ṣe Lé Wọn Padà Lọ Sí Ìlú Wọn Pẹ̀lú…
Super Eagles àti Àwọn agbabọọlu Cameroon tí a tun mọ wọn sí Indomitable Lion bẹrẹ ere bọọlu ti ipele ofìdí rẹmi, o gba ilé rẹ̀ẹ lọ ti ẹlẹyinbo n pe n Knock Out ní dede aago mẹsan-an alẹ́
Ajayi ọmọ ẹgbẹ́ Agbábọ̀ọ̀lù Super Eagles lo…
Akọ̀wé America Yín Ìbáṣepọ̀ Orílẹ̀-èdè Rẹ̀ Pẹ̀lú Angola
Akọ̀wé tí America Antony Blinken tí yín ìbáṣepọ̀ láàrín Orílẹ̀-èdè America àti Orílẹ̀-èdè Angola, Ó sọ pé ìbáṣepọ̀ náà tí dé ibì gíga, Ó sọ èyí làkókò àbẹwò rẹ̀ sí Luanda.
Blinken sọ pé òun tí jíròrò lórí rògbòdìyàn tó wà láàrín Rwanda…
Ilé Iṣẹ́ Ọkọ̀ Òfúrufú Boeing Gbà Pé Àwọn Se Àsìse Látàrí Ilẹ̀kùn Tó Fò Yọ
Ọgá Ilé Iṣẹ́ Ọkọ̀ Òfurufú Boeing ti sọ pé awon gba pe àwọn se àsìse látàrí ilẹ̀kùn tó fò yọ ni kété ti ọkọ Òfúrufú gbéra ni orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Bótilẹ̀jẹ́pé kò sí ẹni tó fára pa nígbà tí ìsèlè náà ṣẹlẹ̀ ni ọjọ́ Ẹtì. Ìjọba…
Wọ́n Ṣé Ìwọ́de Kẹdùn Àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Palestine Ní Casablanca
Àwọn aráàlú Morocco ṣé iwọde ní àtìlẹ́yìn àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Palestine ní Casablanca, wọ́n n pé láti fòpin sí rògbòdìyàn Gaza, kí ìjọba Orílẹ̀-èdè Morocco sí fòpin sí ìbaṣepọ̀ wọ́n pẹ̀lú Israeli.
Ẹgbẹẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹẹgbẹ̀rún ló gba…
Ẹgbẹ́ Aláàdáni Rọ Ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko Láti Fàyè Gba Ètò Ìdìwò Nípa Ìlera.
Ẹgbẹ́ Aláàdáni lórí ọ̀rọ̀ ìlera, ti rọ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko láti faye gba ètò Ìdìwò nipa ìtọjú ìlera, wọn ní eleyii yóò mú kí àwọn tó kún diẹ fún leè ba tójú ara wọn
Ọ̀rọ̀ yìí jáde níbi ìpàdé àwọn òṣìṣẹ́ ìlera ní Ikeja ni ilu Eko
Ààrẹ…
Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin ECOWAS Pé Fún Ìgbìyànjú Látí Kojú Ìpènijà Ààbò
Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin tí àwọn Orílẹ̀-èdè ní Ìwọ̀-oòrùn Áfíríkà (ECOWAS), tí bẹ̀rẹ̀ ìpàdé Aṣojú Kejì rẹ̀ tí ọdún 2023, pẹ̀lú ìpè fún ètò ìdáàbòbò àyíká àtí àgbègbè láti kojú Ìpènijà ààbò àgbègbè náà.
Àpéjọ náà tún wà fún ìjíròrò lórí àwọn…