Browsing Category
Ìròyìn Àyíká
Ìjà Ìgboro Agbègbè Sọ Mẹ́ẹ̀dógún Ènìyàn Dolóògbé, Mẹ́rìndínlógún Farapa Ní Gúsù Sudan
Ó kéré tán ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún ti dágbére f'áyé tí mérìndínlógún míràn sì tún farapa nínú àwọn ikọ̀lù ìjà Ìgboro agbègbè ní Tonj South County, Warrap State, Ariwa South Sudan, ẹnìkan sọ èyí ní ọjó Ẹtì.
Kọmísọ́nà Tonj South County, Ring…
Ìdìbò Ọdún 2027: Ẹgbẹ́ Òṣèlú Labour Party Kòní Darapọ̀ Mọ́ Ẹgbẹ́ Mìíràn
Ẹgbẹ́ Òṣèlú Labour Party ti sọ pé àwọn koni darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ míràn ninu ìbò gbogbogbòò ọdún 2027.
Èyí jẹ ọkan lára kókó méjìlá àlàkalẹ̀ ìpinnu níbi Ìpàdé National Executive Council (NEC) ti wọn ṣe ní ọjó Ẹtì ní ìlú Abuja.
Nigba ti o…
Àjọ NUPEC Gbáradì Láti Dá Ààbò Bo Àwọn Ibi Ìwakùsà
Àjọ National Unity and Peace Corps, NUPEC sọ pé àwọn ti ṣetán ju àtẹ̀yìn wá lọ láti fi ààbò bo àwọn ibi Ìwakùsà káàkiri orílẹ̀-èdè yìí látàrí ìwé àbádòfin Ìfilọ́lẹ̀ tó de àjọ náà ti wọ́n yóò buwọ́lù.
Ọ̀gá àgbà patapata àjọ náà,…
Ìṣòro Ojú Ọjọ́: Ààrẹ Gba Àwọn Olórí Àgbáyé Nímọ̀ràn Láti Wà Ní Ìṣọ̀kan
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti gba àwọn adari agbaye nímọ̀ràn láti wà ní isokan, ní emi ìgboyà àti kí wọn ní ẹ̀mí ifaraji láti ṣàkóso ìṣòro oju ọjó lágbáyé tó n buru síi.
Ààrẹ sọ eyi ní ọjó ojoru nibi Ipade apero láti ori…
Mínísítà Àṣà Kí Àlàáfín Tuntun Ti Ìlú Ọ̀yọ́ Kú Oríire
Mínísita orílè-èdè yìí fún àṣà, iṣẹ, Ìrìn-àjò òun igbafe àti ọgbọ́n àtinúdá ọrọ̀ ajé, Hannatu Musawa ti kí Àlàáfín tuntun ti Ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Abimbola Akeem Owoade, kú oríire, ti ìgorí ìtẹ́ baba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Aláàfin…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra Fi Orí Ọ̀nà Àbálọ Sí Pápákọ̀ Òfúrufú Sọ Orúkọ Gómìnà Tẹ́lẹ̀rí Láti Bu Ọlá Fún
Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, ọjọgbọn, Chukwuma Soludo
ti sọ ọ̀nà tó lọ sí pápákọ̀ òfurufú Chinua Achebe ní ìlú Umueri ní- “Willie Obiano Boulevard,” láti fi bù ọlá fun Gómìnà àná -Chief Willie Obiano.
Ìkéde yìí wáyé níbi ayẹyẹ…
Ijóba Ipinlẹ Kwara Múra Sí Ìgbógun Ti Ìgbọ̀nsẹ̀ Ṣíṣe Ní Ìta Gbangba
Ijóba Ìpínlẹ̀ Kwara ti fi dá àwọn ènìyàn rẹ̀ lójú pé òun yoo se ise òun bí iṣẹ́ nípa líla àwọn ènìyàn lọ́yẹ̀ ewu tó wà ninú ki àwọn kan máa se ìgbọ̀nsẹ̀ síta gbangba káàkiri.
Nígbàtí ó ń bá àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀, ọ̀gá àgbà Ilé iṣẹ Kwara…
Olùdarí Aṣòfin Èkó Rọ Àwọn Agbóhùnsáfẹ̀fẹ́ Orí Rédíò Láti Máa La Àwọn Ará Ìlú Lọ́yẹ̀ Nípa Ọ̀rọ̀…
Olùdarí Ilé Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó, Aṣòfin Mojísọ́lá Lasbat Meranda ti rọ àwọn Agbóhùnsáfẹ̀fẹ́ orí rédíò láti tẹ̀ síwájú nínú akitiyan wọn láti máa la àwọn ará ìlú lọ́yẹ̀ nípa ọ̀rọ̀ àyípadà ojú-ọjọ́
Nígbà tí ó ń kí àwọn òṣìṣẹ̀…
Ìpínlẹ̀ Kogi: Àjọ ECHO Pín Nǹkan Ìrọ̀rùn Fún Àwọn Tí Omíyalé Se Lọ́sẹ́
Àjọ international organisation, the European Civil Protection and Humanitarian Aid Operations (ECHO ti pin nǹkan ìrọ̀rùn fún olùgbé ọgọ́rùn ún le ẹgbẹ̀rún ti wọn fara kásá nínú iṣẹlẹ Omíyalé tó wáyé ni ọdún to kọjá ni ìpínlẹ̀…
Bísọ́ọ̀bù Àgbà Kaigama Pé Fún Aláàfia, Ìṣọ̀kan Nínú Ọ̀rọ̀ Rẹ̀ Fún Ọdún Tuntun
Bísọ́ọ̀bù Àgbà ti ìjọ Kátólìkì, ẹni ọ̀wọ̀ Dókítà Ignatius Kaigama ti ní ìrètí àti ọjọ́ ọ̀la tó dára fún odún 2025, Ó wá pè àwọn ọmọ Nàìjíríà láti wá ni ìfé, isọ̀kan àsọyépọ̀ ẹlẹsin jẹ̀sìn to dára ni orílẹ̀-èdè yìí
Bísọ́ọ̀bù Àgbà,…