Ààrẹ Muhammadu Buhari Ti Búra Fún Adájọ́ Àgbà Ilẹ̀ Nàìjíríà
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti búra fún adájọ́ àgbà Olukayọde Ariwoọla gẹ́gẹ́ bíi adájọ́ àgbà ilẹ̀ Nàìjíríà. Ètò náà wáyé ní ọjọ́rú pẹ̀lú ayẹyẹ ráńpẹ́ ní gbọ̀ngàn ilé ìjọba àpapọ̀ síwájú ìkéde ọlọ́sẹ̀-ọ̀sẹ̀ ti…