Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà Rọ Àwọn Ọmọ Nàìjíríà Láti Gbá Àlàáfíà Láàyè Níbí Ètò Ìdìbò Gbogbogbò…

Ààrẹ Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ahmad Lawan tí rọ̀ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti ṣé jẹ́jẹ́ níbi ìdìbò gbogbogbò tó ń bọ̀. Sẹnetọ̀ Lawan tún rọ wọ́n látí wà sí àgọ́ ìdìbò wọ́n ní àwọn ọjọ́ tí á yà sọtọ fún Ìbò kí…

Ilé-iṣẹ́ Agbofinro Lórí Òògùn Olóró Gbà Àwọn Òògùn Àìtọ́ Náà Ní Pápákọ̀ Òfurufú Ìpínlẹ̀ Èkó Àtí…

Ilé-iṣẹ́ tó ń gbógun tí òògùn olóró ní Nàìjíríà (Nigeria Drug Law and Enforcement Agency NDLEA) tí gbá áwọn ẹrú òògùn olóró tí wón kó lọ́ sí United Kingdom, Saudi Arabia, New Zealand àtí Cyprus ní àwọn pápákọ̀ òfurufú nlá méjì ní…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna Tí Kìlọ Fún Àwọn Aráàlú Látí Yàgò Fún Irúfìn

Ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna sọ pé àwọn tí gbá áwọn ìjàbọ̀ lórí àwọn ẹgbẹ́ aráàlú kàn tó ń gbèrò láti ṣé ìwọdé lójú òpópó-ònà tó lé kóbá àlàáfíà àti ètò ìlú. Nítorí náà ìjọ̀ba tí gbà àwọn aráàlú níyànjú láti yàgò fún irúfẹ́ bẹ́ẹ̀, ó sí kílọ…

IWD 2023: DC, UN, UNDP Ṣé Ìsàmì Ayẹyẹ Àwọn Obìrin Nàìjíríà Pẹ̀lú Àmì-Ẹrí

Ìránṣẹ́ Orílẹ̀-èdè America sí Nàìjíríà, ní alẹ́ ọjọ́ Àbámẹ́ta, gbá àlejò ìsàmì sí ayajọ ọjọ́ àwọn obìnrin ẹlẹẹkeji irú rẹ̀ pẹ̀lú àwọ́ọ̀dù látí ṣé koriya fún àwọn obìnrin Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lórí ìdàgbàsókè ìlú àtí àwọn ọmọ Obìnrin. Èyí…

Ilé-ẹ̀kọ́ Gíga Àwọn Ọmọ-ogún Nàìjíríà Tí Kọ́ Àwọn Ọjẹ̀-wẹ́wẹ́ Ilé-ẹ̀kọ́ Náà Ní Ìjà Ojú Omí

Ilé-ẹ̀kọ́ gíga àwọn ọmọ-ògún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NDA), tí ṣètò ìkẹ́kọ̀ lórí omí fún ọgọrùn lé ní ọgọrin àwọn ọmọ ilé-ìwé náà ní ìpínlẹ̀ Kaduna. Alákóso NDA, Major General Ibrahim Yusuf sọ́ èyí dì mímọ̀ làkókò tó ń bá àwọn akọroyin…
button