Ọmọ Orílẹ̀-èdè America Kàn Gbá Òmìnira Ni Orílẹ̀-èdè Saudi Arabia
Àwọn aláṣẹ Saudi tí ṣé ìtùsílẹ̀ ọmọ orílẹ̀-èdè America kàn Saad Ibrahim Almadi ní ọjọ́ Ìṣẹgun tí wọ́n rán lẹ́wọn fún ọdún mokandinlogun 19 fún àtakò ìjọba orílẹ̀-èdè náà lórí ẹ̀rọ́ Twitter rẹ̀ ṣùgbọ́n kò ní ànfàní láti fí orílẹ̀-èdè náà…