Take a fresh look at your lifestyle.

Ìjọba Nàìjíríà Kéde Ọjọ́ Kínní Oṣù Karùn-ún, Ọdún Yìí Fún Ìsinmi Àwọn Òṣìṣẹ́

Ìjọba Nàìjíríà tí kéde Ọjọ́bọ̀, ọjọ́ kínní oṣù kàrún, ọdún 2025 gẹ́gẹ́bí ọjọ́ ìsinmi fún gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ jákèjádò Orílẹ̀-èdè látí samisi Ayẹyẹ Ọjọ́ Àwọn òṣìṣẹ́ tí ọdún yìí. ‎ ‎ Mínísítà fún ètò abẹ́lé, Dókítà Olubunmi Tunji-Ojo, tó…

Gómìnà Katsina Gbóríyìn Fún Àwọn Ẹṣọ Aláàbò Òfurufú Ìwọ̀-oòrùn Àríwá ‎

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Katsina, Malam Dikko Umaru Radda, tí ṣé àbẹwò pàtàkì kán sí ẹgbẹ́ Àwọn Ológun òfurufú tó ń ṣiṣẹ́ nínú ètò ààbò tí wọ́n pé ní Fansan Yamma ní Katsina níbí tó tí ń yìn àwọn ipá wọ́n nínú iṣẹ́ ààbò tí ìwọ̀-oòrùn àríwá. ‎ ‎…

Mínísítà Rọ́ Àwọn Ilé-ìwé Gíga Tí Ẹ̀kọ́ Látí F’ayé Gbá Àṣẹ Ìwé Ẹrí Méjì

Mínísítà tí ètò Ẹ̀kọ́, Maruf Alausa tí rọ́ àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí Ẹ̀kọ́ látí f'ayé gbá ìmọ túntún àti àṣẹ ìwé ẹrí onígbá méjì, èyítí o fún wọ́n láàyè àwọn ọmọ ilé-ẹ̀kọ́ ní ìwé ẹrí oríṣi méjì bíi "Ìmọ̀-ẹrọ́ (B. Sc.) àti ìwé ẹrí Ẹkọ (NCE).…

Mínísítà Gbóríyìn Fún Àwọn Ẹṣọ Ghana Kán Fún Ìgbàlà Àwọn Ọmọ Nàìjíríà Ogún-lugba-Dín-Kán

Mínísítà fún Ìpínlẹ̀ fún ètò Ọrọ òkèèrè, Bianca Odumegwu-Ojukwu, tí gbóríyìn fún àwọn aláṣẹ orílẹ-èdè Ghana fún Ìgbàlà àwọn ọdọ Nàìjíríà Ogún-lugba-Dín-Kán (219) tí wọ́n gbé lọsí orílẹ-èdè Ìwọ̀-oòrùn Áfíríkà náà tí wọ́n sí fí ipá mú wọ́n…

Gómìnà Adamawa Ṣé Ìlérí Àtìlẹ́yìn Fún Àwọn Ilé-iṣẹ́ Ìbílẹ̀

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Adamawa, Ahmadu Fintiri, tí tún fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ sí látí ṣé àtìlẹ́yìn fún àwọn ilé-iṣẹ́ ìbílẹ̀ fún pàtàkì ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ náà àti Orílẹ̀-èdè lápapò. ‎ ‎ Gómìnà sọ èyí dí mímọ̀ l'àkókò ayẹyẹ Ọjọ́ Ọdún àpapọ̀ Nnoma-Jhar…
button