Àjọ Élétó Ìdìbò INEC Ṣètò Àwọn Ìgbìmọ̀ Látí Ṣé Àtúnyẹwò Àwọn Ìdìbò Gbogbogbò Tó Kọjá
Àjọ élétó ìdìbò tí Orílẹ̀-èdè yìí INEC tí ṣètò àwọn ìgbìmọ̀ inú-ilé méjì látí ṣé àtúnyẹwò àtí ṣé àkọsílẹ̀ àwọn iṣẹ́ tí Ìdìbò Gbogbogbò 2023.
Alága Àjọ náà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu ṣé ìfilọ́lẹ̀ àwọn ìgbìmọ̀ náà ní Ọjọ́rú ní Abuja,…