Take a fresh look at your lifestyle.

Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Tí Ṣé Tán Láti Fi Orúkọ Àwọn Onífẹ̀yìntì Sílẹ̀ Fún Ètò Ìlera Ìpínlẹ̀ Náà

Gómìnà Ademola Adeleke tí Ìpínlẹ̀ Osun tí kéde pé àwọn òṣìṣẹ́ fẹ̀yìntì ní ìpínlẹ̀ náà yóò ní ànfààní nínú ètò iṣeduro ìlera ní Osun. Adeleke ṣé ìtọ́kasí yìí làkókò tí o ngbà àwọn aṣáájú kàn ní àlejò fún ọdún Iléyá ní ilé rẹ̀ ní Ede.…

Àwọn Àrìnrìn-Àjò Mùsùlùmí Tó Ṣójú Ìjọba FCT Nínú Hajj Tó Parí, Gbàdúrà Fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà

Àwọn aṣojú ìjọba àrìnrìn-àjò Mùsùlùmí tí Abuja, Olú-ìlú Nàìjíríà, FCT, to rìn ìrìn-àjò lọ́ sí Saudi Arabia fún iṣé Hajj, tí parí Hajj wọ́n. Alága tí àwọn àrìnrìn-àjò náà tí wọ́n pé ní "Ministerial task team to 2023 Hajj operations"…

Ìgbìmọ̀ Tó Ń Dárí Àwọn Ilé-ẹ̀kọ́ Gíga Fí Ipò Wọ́n Múlẹ̀ Lórí Gbígbà Àwọn Ọmọ Ilé-ìwé Wọ́lé

Ìgbìmọ̀ tó ń dárí àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí Orílẹ̀-èdè (Nigeria University Commission NUC) tí fí ìdí ipò rẹ̀ múlẹ̀ lórí àwọn Ìlànà ìwọlé sí ilé-ìwé gíga Fásítì pẹ̀lú òye àmì tó kéré jù (Core Curriculum Minimum Academic Standard CCMAS) bó tí…
button