Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Nàìjíríà Tí Fọwọ́sí Àwọn Ìwé-àṣẹ Àṣẹ Mẹ́rin Kàn

Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí buwọ́lù àwọn ìwé-aṣẹ mẹ́rin ní ìbámu pẹ̀lú ìlérí rẹ̀ tó ṣé fún àwọn ọmọ Nàìjíríà ní ọjọ́ iburasipo rẹ̀ Olùdámọ̀ràn pàtàkì sí Ààrẹ lórí àwọn iṣẹ́ pàtàkì, Ibaraẹnisọrọ àtí Ìlànà, Ọ̀gbẹ́ni Dele Alake ṣé àfihàn…

Ààrẹ Tinubu Dá Owó-Orí Dúró Lórí Àwọn Ilé-iṣẹ́ Ẹrọ Ìbánisọ́rọ́

Ààrẹ Bola Tinubu tí fọwọ́ sí dídádúró tí ìpín márùn-ún nínú ọgọ́rùn-ún owó-orí "Excise Tax" lórí ilé-iṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó tún ti fọwọ́sí ìdádúró owó-orí "Excise Duty" tí àwọn ilé-iṣẹ́ ilẹ̀ wà. Olùdámọ̀ràn pàtàkì…

Ìpínlẹ̀ Èkó Ṣétán Látí Tíi Àwọn Ilé Tí Kò Ní Àpótí Ìdàlẹ̀nù Tó Yẹ́

Àjọ tó ń ṣètò ẹ̀gbin ní ìpínlẹ̀ Èkó, LAWMA tí sọ pé àwọn yóò bèrè sí ní tíì àwọn ilé tí wọ́n kò ní àpótí ìdọ̀tí ní Lagos Island àtí Lagos Mainland, bẹ̀rẹ̀ làti ọjọ keje oṣù keje ọdún 2023. Èyí ló wáyé ṣáájú Ìkìlọ tí wọ́n tí sí àwọn…

Àwọn Aláṣẹ Ìgbìmọ̀ Ẹ̀kọ́ Tí Gbá Àwọn Alágbàṣe Nímọ̀ràn Iṣẹ́ Àkànṣe Tó Dára

Ìgbìmọ̀ aláṣẹ ètò ẹ̀kọ́ ìpìlẹ tí Ìpínlẹ̀ Nasarawa NSUBEB, tí búra látí gbé ìgbésẹ tó lágbára sí èyíkéyìí alágbàṣe tá ríi pé Ó kùnà tàbí rúfin àwọn àdéhùn iṣẹ́ àkànṣe rẹ̀. Alága àgbà tí Ìgbìmọ̀ náà ní Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Honorable…

Àwọn Kọmisọna Túntún Yóò Wà Lábẹ́ Ìdánwò Olóṣù mẹ́fà – Gómìnà Kano

Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abba Yusuf tí fí gbogbo àwọn Kọmisọna tí wọ́n ṣẹṣẹ yán látí wà lábẹ́ ìdánwò olóṣù mẹ́fà kí wọ́n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní kíkún ní ìpínlẹ̀ náà. Gómìnà sọ èyí ní ìlú Kano làkókò tó ń dárí ìpàdé ìgbìmọ̀ àwọn aláṣẹ tí Ìpínlẹ̀…

Nàìjíríà Yóò Tẹ̀síwájú Láti Máa Jẹ́ Aṣíwájú Nílẹ̀ Áfíríkà – Olùrànlọ́wọ́ Ààrẹ

Oludamọran pàtàkì fún Ààrẹ Bola Tinubu lórí àwọn iṣẹ́ àkànṣe, Ibaraẹnisọrọ àtí Ìlànà, Dele Alake sọ pé Ààrẹ mọ́ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní wọ́n ń wò gẹ́gẹ́ bí olórí nílẹ̀ Áfríkà, àti pé ó tí múra látí ṣé bó tí tọ́. Alake sọrọ yìí di…
button