Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ekiti Tẹlẹ Gbóríyìn Fún Àwọn Ìgbésẹ̀ Ààrẹ Tinubu
Gómìnà nígbà kàn rí ní ìpínlẹ̀ Ekiti, Ayodele Fayose tí gbóríyìn fún àwọn ìgbésẹ̀ ìgboyà tí Ààrẹ Bola Tinubu ń gbé báyìí.
Nitorinà, Ó ń kési gbogbo ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà látí ṣé àtìlẹ́yìn fún Ààrẹ, nítori wípé "kó lé dá ṣé."…