Take a fresh look at your lifestyle.

Ètò Ń Tẹ̀síwájú Lórí Òṣùwọ̀n Owó Oṣù Tuntun Fún Àwọn Olùkọ́ – NUT

Ẹgbẹ́ àwọn olùkọ́ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (Nigeria's Union of Teachers NUT) sọ pé iṣẹ́ ń lọ lọ́wọ́ lórí òṣùwọ̀n owó oṣù tuntun fún àwọn olùkọ́. Akọ̀wé Àgbà tí ẹgbẹ́ náà, Dókítà Mike Ike-Ene, sọ èyí di mímọ̀ ní Abùjá l'akoko tó ń bá àwọn…

Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Yóò Gbé Ìwé-Ètò Ìṣúná Ọdún 2023 Lọsí Ìlé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àpapọ̀

Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò gbé àwọn àbá ètò ìsúná ọdún 2023 wá ní ọjọ́ Ẹtì, ọjọ́ keje, oṣù kẹwàá ọdún 2022 sí ìpàdé ìpejọ àpapọ̀ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Nàìjíríà, ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè. Ààrẹ ilẹ̀ ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà, Ahmad Lawan sọ…

Ààrẹ Buhari Lerí Láti Jẹ́ Kí Ìjọba Tiwá-ń-tiwá Túbọ̀ Fí Ẹsẹ Múlẹ̀ Sí Ní Ìdìbò 2023

Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ pé ètò ìṣàkóso réré nìkan ló lè ṣèrànwọ́ láti mú ìjọba tiwá-ń-tiwá múlẹ̀ ní Nàìjíríà. Nitorinà o tí ṣé ìlérí láti ríí dájú pé àwọn ìdìbò tó tọ, tí àwọn ará ìlú yóò ní igbẹkẹle nínú rẹ̀ ati tí yóò dájú bí…

Ìdìbò 2023, Ààrẹ Buhari Ń Wàásù Ìpolongo Tó Dà Lórí Ọ̀nà Àbáyọ́

Ààrẹ Muhammadu Buhari tí ṣé itẹwọgbà ipilẹsẹ tí Ìgbìmọ̀ Àlàáfíà tí Orílẹ̀-èdè yìí ṣé bí wọ́n fí ọwọ́ gbogbo awọn olóṣèlú Olùdijé ipò ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà bí ìpolongo ìbó kò ṣé gbọdọ da lori inúnibíni, ẹgàn arà ẹní àti ikọlù. Nínú…
button