Ààrẹ Buhari Pàdà Sí Abùjá
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí pàdà sí Abùjá lẹyìn tó kópa nínú ìpàdé World Bio Summit ní Seoul, orílẹ̀-èdè South Korea.
O balẹ gudẹ sí Papakọ Òfurufú International Nnamdi Azikiwe ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ Ẹtì.
Lára àwọn tí wọ́n pàdé Ààrẹ…