Take a fresh look at your lifestyle.

Àjíǹde: Adarí ilé, Igbákejì rọ àwọn kírísítíẹ́nì láti kọ́ ìṣe kŕisítì

Adarí ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú, ọ̀gbẹ́ni Abbas Tajudeen àti igbákejì rẹ̀ Benjamin Kalu ti rọ àwọn ọmọ lẹ́yìn kírísítí láti kọ́ ìṣe ìfaradà Jésù Kírísítì. Wọn rọ awọn ọmọ Naijiria lati ni ifẹ ara wọn lai bikita ẹya, ẹsin,…

Ilé iṣẹ́ tí ń mójútó Ìrìn àjo lọsí orílẹ̀-èdè mìíràn dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè…

Ilé iṣẹ́ tí ń mójútó Ìrìn àjo lọsí orílẹ̀-èdè mìíràn ní Nàìjíríà (NIS), Aala Agbofinro Illela ti ipinlẹ Sokoto, ti fidiẹ mulẹ pe wọn ti dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Mali méjìlé-lọ́gọ́ta padà lati oju ile Illela.…

Hajj 2025: Eko Ṣonígbọ̀wọ́ àyẹ̀wò ìlera fún àwọn tó fẹ́ rìnrìn àjò mímọ́

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Eko, Ọ̀gbẹ́ni Babajide Olusola Sanwo-Olu àti igbákejì rẹ̀, Dókítà Kadri Hamzat ti Ṣonígbọ̀wọ́ àyẹ̀wò ìlera pataki fún àwọn tó fẹ́ rìnrìn àjò mímọ́ lọ sí orílẹ̀ èdè Saudi Arabia láti ìpínlẹ̀ Eko.…

Àjíǹde: Gómìnà pè fún ìgbàmọ́ra, Ìrẹ́pọ̀ kí Nàìjíríà lè dára jùlọ

Gómìnà Ìpínlẹ Anambra, Ọ̀jọ̀gbọ́n Chukwuma Soludo, kí àwọn ọmọ lẹ́yìn Krísítì kú ọdún Àjíǹde, tí ó sí pè fún ìgbàmọ́ra, Ìrẹ́pọ̀ kí Nàìjíríà lè dára jùlọ. Ninu afiranṣẹ kan lati ọdọ akọwe awọn Akọroyin…
button