Take a fresh look at your lifestyle.

Ilé-iṣẹ́ ìjọba yóò ṣàtúnṣe lórí ìlànà ìwé ìrìnnà Nàìjíríà àti Físà

Ilé-iṣẹ́ ìjọba to n risi ọrọ inu orilẹ-ede ti pinnu lati ṣàtúnṣe lórí ìlànà ìwé ìrìnnà Nàìjíríà àti Físà lati ba ti agbaye ati bi o ṣe n lọ mu, pẹlu iranlọwọ awọn to nii ṣe pataki ni orilẹ-ede. Igbesẹ yii waye lati…

Iṣẹ́ ọ̀gbìn: Nàìjíríà gba owó ìrànlọ́wọ́ Bílíọ́nù kan Dọ́là

Ilé ìfowópamọ́ ìdàgbàsókè Áfíríkà (AfDB), Ilé-ìfowópamọ́ ìdàgbàsókè Mùsùlùmí (IDB) àti owó káríayé fún ìdàgbàsókè ètò ọ̀gbìn ti gbé iye owó Bílíọ́nù kan Dọ́là sílẹ̀ láti túnbọ̀ pèsè abala…

Jonathan rọ àwọn ààrẹ tó ti kọjá kí wọ́n ní ìṣọ̀kan láti dẹ́kun ìnira ará ìlú

Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí, Goodluck Jonathan ti rọ àwọn adarí olóṣèlú àti pàápàá jùlọ àwọn ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó kọjá láti fìmọ̀ ṣọ̀kan kí mẹ̀kúnnù máá baà jìyà. Jonathan tun wa…

Mínísítà fún ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ pè fún ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè lẹ́yìn ìdájọ́…

Mínísítà Nàìjíríà fún ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àti ìfihàn lápapọ̀, Mohammed Idris ti rọ gbogbo ẹgbẹ́ olóṣèlú àti àwọn àgbààgbà ìlú láti mójú kúrò lórí ìdìbò, kí wọn ó sì gbájúmọ́ bí orílẹ̀-èdè yóò…

Gómìnà Gombe bẹnu àtẹ́ lu ìṣekúpa arábìnrin kan, pàṣẹ ìṣèwádìí

Gómìnà  Muhammadu Inuwa Yahaya ti ìpínlẹ̀  Gombe ti bẹnu àtẹ́ lu ìṣekúpa Aishatu Abdullahi, tí ó jẹ́ ẹni ọdún méjìdín-lọ́gọ́ta, ti ojúlé kẹjọ ní agbègbè Jekadafari , ní ìgboro Gombe, tí ó sì ṣe àpèjúwe ìṣẹ̀lẹ̀…

Ààrẹ Tinubu ń darí àpèjọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ àpapọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹta

Ààrẹ Bọla Tinubu ń darí àpèjọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ àpapọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹta ti ìjọba rẹ̀ ní gbọ̀ngàn ilé 0rílẹ̀-èdè, Abuja. Apejọ naa, eyi ti o bẹrẹ ni nnkan bii agogo mẹwaa owurọ ni Akọwe fun ijọba apapọ, George Akume; Ọga agba fun…
button