Ààrẹ Tinubu yóò bá orílẹ̀-èdè sọ̀rọ̀ ní ọjọ́ kìnníí ọdún tuntun
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu yóò bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ jákèjádò lórí afẹ́fẹ́, ní ọjọ́ Ajé, ọjọ́ kìnníí ọdún tuntun 2024.
Alaye kan lati ọdọ agbẹnusọ aarẹ, Ajuri Ngelale, sọ pe aarẹ yóò bá orílẹ̀-èdè sọ̀rọ̀ ni…