Take a fresh look at your lifestyle.

Ìjọba àpapọ̀ fọwọ́sí iye owó tó tó bílíọ́nù méjì ààbọ̀ Náírà fún abala nǹkan…

Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ  àpapọ̀ ti fọwọ́sí iye owó tótó  bílíọ́nù méjì àbọ̀ Náírà fún ríra àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn irúgbìn, láti pèsè nǹkan ọ̀gbìn lọ́pọ̀ yanturu  ní orílẹ̀-èdè. Minisita fun eto ọgbin, Mustapha Shehuri…

NDP 2021-2025: Ìgbìmọ̀ Àwọn Gómìnà Nàìjíríà gbóríyìn fún Ààrẹ Bùhárí

Ìgbìmọ̀ Àwọn gómìnà gbórìyìn fún ààrẹ Mùhámmádù Bùhárí fún fífún orílẹ̀-èdè ní ètò ìdàgbàsókè  titun. Nigbati o n ba   Awọn oniroyin Ile-igbimọ sọrọ  nibi ti o ti nṣoju  awọn ẹlẹgbẹ rẹ, ni kete lẹhin…

Ààrẹ Bùhárí bẹnu àtẹ́ lu ìpànìyàn tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Násáráwá

Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fi ìbànújẹ́ hàn lórí ìpànìyàn tí  o mẹmi  àwọn àgbẹ̀ márùnlé-lógójì lọ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ sì farapa lẹ́yìn ìkọlù tó tún wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ Lafia, Obi àti Awe ní ìpínlẹ̀ Nasarawa. Nínú ọ̀rọ̀ kan tí Ààrẹ Buhari fi…

Nàìjíríà Ṣe ìfilọ́lẹ̀ Ojú òpó wẹ́ẹ́bù ìkẹ́kọ̀ọ́

Ìjọba Nàìjíríà ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ ojú òpó wẹ́ẹ́bù ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ kan tí a pè ní “inspire.education.gov.ng” fún gbogbo àwọn ipele ètò-ẹ̀kọ láti kẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ìrọ̀rùn. Aṣoju  Akọwe agba ti Ile-iṣẹ Ẹkọ apapọ, Minisita fun…

Mínísítà rọ àwọn tó fẹ́ gba ìwé ìrìnnà láti máá gba ọ̀nà ẹ̀bùrú

Ìjọba Àpapọ̀ ti kìlọ̀ fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí wọ́n ń bèèrè fún ìwé ìrìnnà káríayé láti yàgò fún àwọn onímọ̀dàrú àti àwọn tí wọ́n ṣe àpèjúwe wọn gẹ́gẹ́ bí àwọn òṣìṣẹ́ aláìlóòtọ́,…

Àsàbà yóò ṣagbátẹrù àjọ̀dún eré ìdárayá àpapọ̀ ọdún fún 2022

Ìgbìmọ̀  Orílẹ̀-èdè lórí Àwọn eré ìdárayá ti fọwọ́sí Oṣù kọkànlá ọjọ́ kejì sí ìkẹẹ̀dógún, ọdún 2022 ,gẹ́gẹ́ bí àwọn ọjọ́ tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fùn àjọ̀dún  àpapọ̀ eré ìdárayá ẹlẹ́ẹ̀kọkànlé-lógún  ní…
button