‘Èmi yóò ri pé ìjọba ìbílẹ̀ ní òmìnira’,Hon.Abdulaziz
Ọmọ ẹgbẹ́ kan tó ń sojú agbègbè Keffi East, ní Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Násáráwá, Hon Abdulaziz Danladi, ti fi dá àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ Keffi lójú pé òun múratán láti gbárùkù mọ́ ẹ̀tọ́ ìjọba ìbílẹ̀.…