Àwọn ènìyàn márùnlé-lọ́gọ́jọ míràn tún ti ní ààrùn covid
Àwọn ènìyàn márùnlé-lọ́gọ́jọ míràn ló tún ti ní ààrùn covid jákèjádò orílẹ̀-èdè.
Ile-iṣẹ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) lo so eleyii di mimọ lori boṣe n lọ lojoojumọ.
Ile-iṣẹ naa sọ pe awọn eniyan…