Take a fresh look at your lifestyle.

Gómìnà Kwara pàdánù Ọ̀gá Àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ AbdulKadir Mahe

 Ọ̀gá Àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ (CoS) fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara, Ọmọọba AbdulKadir Mahe, ti jẹ́pè olúwa. Ó jẹ́pè olúwa ní àárọ kùtù ọjọ́ Àbámẹ́ta. Ọ̀gá àgbà Akọ̀wé sí Gómìnà, Mallam Rafiu Ajakaye, ní ó kéde…

Igbákejì Ààrẹ Shettima kẹ́dùn pẹ̀lú Gómìnà Ìpínlẹ̀ Jigawa lórí Àjálù méjì tó…

Ààrẹ Bọla Tinubu ti yan àwọn asojú kan tí Igbákejì Ààrẹ Kashim Shettima ṣadarí, láti ṣe àbẹ̀wò ìkẹ́dùn sí Gómìnà àti àwọn ènìyàn Jigawa lórí ikú ìyá àti ọmọkùnrin  Gómìnà ìpínlẹ̀ náà, Alhaji Umar…

Ààrẹ Tinubu ṣèdárò pẹ̀lu IPI, NUJ, àti àwọn mìíràn lórí ikú Rafatu Salami

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti ṣèdárò pẹ̀lú Ẹgbẹ́ àwọn akọ̀ròyìn Nàìjíríà (NUJ) lórí ìpapòdà Hajiya Rafat Onyeche Salami, tí ó jẹ́ Akápò Àjọ àwọn Akọ̀ròyìn Káríayé ní Nàìjíríà (IPI). Ààrẹ wá rọ àwọn…

ASUP sún ìyanṣélódì jákèjádò orilẹ-ede tí ilé èkọ́ gíga gbogbonṣe fẹ́ rawọ́lé…

Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ olùkọ́ni ilé ẹ̀kọ́ gíga gbogbonìṣe (ASUP), ti sún ìyanṣẹ́lódì tí wọ́n ń gbìmọ̀ láti rawọ́lé, léyìí tí ó yẹ kó bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ kọkànlé-lógún, oṣù kẹwàá ọdún  2024. Iyanṣẹ lodi naa yoo bẹrẹ…

Adarí NYSC kí Mínísítà fún ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́ tuntun Ayọdele Ọlawande kú oríire

Adarí gbogbogbò fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Àgùnbánirọ̀ (NYSC), Ajagun Yushau Dogara Ahmed, ti kí Minisita tuntun fún ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́, Ọ̀gbẹ́ni Ayodele Olawande, kú oríire bí Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ṣe yàn àn sí ipò…

Kaduna: Ààrẹ Tinubu pàṣẹ kí àwọn elétò ààbò wá àwọn ọmọ ilé ìwé tí wọ́n jígbé rí

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu, ti dari  àwọn elétò ààbò ní Nàìjíríà láti sa gbogbo ipá wọn ní ṣíṣàwárí àwọn ọmọ ilé ìwé àti olùkọ́ ilé ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti gíga ti Kuriga, ìpínlẹ̀ Kaduna, tí wọ́n jígbé ní…
button