Take a fresh look at your lifestyle.

Olùkọ́ Ilé Ẹ̀kọ́ Gíga Fasiti Kan Ti Ké Sí Ìjọba Láti Ṣe Àmúlò Àṣà ìṣèjọba Àwa-ara-wa

Ọ̀mọ̀we Bayonle Busari ti ilé ẹ̀kọ́ gíga Fasiti Lead City, ni ìlú Ìbàdàn ti ké sí gbogbo ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà láti dìde pẹ̀lú ohùn kan láti sọ fún àwọn adarí wọn kí wọn ṣe àmúlò àṣà ìṣèjọba àwa-ara-wa gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe n ṣe ni Orilẹ èdè…

Aò Ni Fàaye Gba Ilé Ẹ̀kọ́ Tíò kúnjú Oṣuwọn: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣèlérí láti ṣiṣẹ́ papọ̀ pẹ̀lú àwọn Akọwe àti Adarí ilé ẹ̀kọ́ ní tìlú-tòòró àwọn Ìjọba Ìbílẹ̀ láti ti àwọn ilé ẹ̀kọ́ Alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tí kò kúnjú òṣùwọ̀n pa ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Kọmísánnà fún Ètò Ẹ̀kọ́, Sáyẹnsì àti Ìmọ̀…

Ìpèsè Ohun Amáyédẹrùn: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Pe Fún Ìkúnlọ́wọ́ Àwọn Ilé Iṣẹ́ Aládàáni

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti rọ àwọn ilé-iṣẹ́ aládàáni láti máa kún ìjọba lọ́wọ̀ lórí iṣẹ́ ìdàgbàsókè àwùjọ àti ìgbáyégbádùn ará ìlú. Alága ìjọba Ìbílẹ̀ Ìlà-Oòrun Ìbàràpá Olugbenga Abiodun Ọbalọwọ ló sọ̀rọ̀ náà lórúkọ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́,…

Àjọ EFCC Fí Ojú Ọmọ Ilé Ẹ̀kọ́ Gíga Mọ́kànlá Ba Ilé Ẹjọ́ Fún Ẹ̀sùn Jìbìtì Orí Ẹ̀rọ Ayélujára

Àjọ EFCC, Ẹkùn Ìbàdàn ti fi ojú àwọn ọmọ ilé ẹ̀kọ́ gíga Obafemi Awolowo ni Ile-Ifẹ Mọ́kànlá ba ilé ẹjọ́ látàrí ẹ̀sùn jibiti orí ẹ̀rọ ayélujára tí àjọ náà fi kan wọn. Àwọn Mọ́kànlá yìí tíì ṣe ara àwọn afurasí oníjìbìtì orí ẹ̀rọ ayélujára…

Idahun Sì Ìfẹ̀hónúhàn Ẹgbẹ́ Òṣìṣẹ́ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́: Gómìnà Makinde Mú Inú Òṣìṣẹ́ Dùn

Gẹ́gẹ́ ara ọ̀nà lati bù òróró ìtura sí inira àwọn òṣìṣẹ́ ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Gómìnà Seyi Makinde tí ṣèlérí láti san Ẹgbẹ̀rún Mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n Náírà fun àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba àti Ẹgbẹ̀rún Mẹ́ẹ̀dógún fún àwọn òṣìṣẹ́ fẹ̀yìntì. Makinde ló sọ èyí…

Ìkọlù Ẹgbẹ́ Òṣìṣẹ́ Ní Ìpínlẹ̀ Imo: Gbajugbaja Nínú Ẹgbẹ́ Òṣèlú NNPP Ke Sì Àwọn Agbófinró Láti Fi Ojú…

Gbajúgbajà nínú ẹgbẹ́ òṣèlú NNPP tó tún jẹ́ bàbá isalẹ fún ẹgbẹ́ Akọ̀ròyìn ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ (Oyo State Correspondents' Chapel) Olufemi Ajadi Oguntoyinbo tí korò ojú sí ìkọlù sí Ààrẹ ẹgbẹ́ oṣiṣẹ Joe Ajero lásìkò tí òun àti ẹgbẹ́ oṣiṣẹ ni…

Oníjìbìtì Orí Ẹ̀rọ Ayélujára Mọ́kànlélógójí Di Èrò Ẹ̀wọ̀n Ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Àti Ògùn

Kò dín ní Mọ́kànlélógójí afurasí oníjìbìtì orí ẹ̀rọ ayélujára ló ti di ẹ̀rọ ẹ̀wọn lẹ́yìn ti ìwádìí fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé wọ́n jẹ̀bi ẹ̀sùn ti Àjọ EFCC fi kàn wọ́n. Àwọn afurasí oníjìbìtì orí ẹ̀rọ ayélujára tó jẹ̀bi ẹ̀sùn tí Àjọ EFCC, Ẹkùn tí…

Jìbìtì Orí Ẹ̀rọ Ayélujára: Ọwọ́ Àjọ EFCC Tẹ Afurasí Mọ́kándínláàdọ́rin Ní Ilé-Ifè

Ọwọ́ sìnkún Àjọ EFCC, Ẹkùn Ìbàdàn ti tẹ afurasí oníjìbìtì orí ẹ̀rọ ayélujára Mọ́kándínláàdọ́rin (69) ni Ile-ifẹ ní Ipinlẹ Ọ̀ṣun. Àtẹ̀jáde láti ọwọ́ Olórí ẹ̀ka ìròyìn àti ìkéde fún Àjọ EFCC, Ekun Ìbàdàn, Dele Oyewale ló ṣàlàyé pé, ọwọ́…
button