Take a fresh look at your lifestyle.

Ìsọ̀kan Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ní Ẹkun Gúsù Ìwọ̀ Oòrùn Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà: Makinde Àti Adeleke Fẹnu Kò

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ S'eyi Makinde àti Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Ademola Adeleke ti ṣèlérí láti fọwọ́sowọ́pọ̀ fún ìṣọ̀kan ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ni Ẹkùn Gúsù Ìwọ̀ Oòrùn.. Nígbà tó n sọrọ lórí ìdí pàtàkì tó fi ṣe ibẹwo sí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́,…

Makinde Yan Fola Oyekunle Gẹ́gẹ́ Bíi Makinde Yan Folu Oyekunle Gẹ́gẹ́ Bíi Igbákejì Olórí Òṣìṣẹ́ Rẹ

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi ọwọ sí ìyànsípò Fola Oyekunle gẹ́gẹ́ bíi igbákejì olórí òṣìṣẹ́ rẹ̀. Oyekunle náà ló jẹ́ ọkan lára àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Kẹsán sojú Ẹkùn Àríwá Ìbàdàn kínní (Ìbàdàn North 1), nibi tó ti jẹ́…

Ètò Ìforúkọsílẹ̀ Àti Ààbò: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ṣe Ìpàdé Ìṣínilétí Fún Àwọn Oníkẹ̀kẹ́ Alùpùpù…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣe ìpàdé ìṣínilétí ọlọ́jọ́ kan fún àwọn Oníkẹ̀kẹ́ Alùpùpù tí wọn n pe ní Ọ̀kadà àti Kẹ̀kẹ́ ẹlẹsẹ mẹta (Kẹ̀kẹ́ Napep) lórí pàtàkì ṣíṣe ìforúkọsílẹ̀ Kẹ̀kẹ́ àti Ọ̀kadà jákèjádò Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́. Ẹni tíì ṣe Kọmísánnà fún…

Ilé Ẹjọ́ Rán Òníjìbìtì Orí Ẹ̀rọ Ayélujára Métàlélọ́gbọ̀n Lọ Ọgbà Ẹ̀wọ̀n Ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Àti Ògùn

Àjọ to n gbógun ti ṣíṣe owó ìlú kúmọkùmọ, EFCC, Ẹkùn tí Ìbàdàn tí taari àwọn oníjìbìtì orí ẹ̀rọ ayélujára Métàlélọ́gbọ̀n lọ sí ọgbà ẹwọn ní ìbámu pẹ̀lú ẹ̀sùn ti ilé ẹjọ́ ká sí wọn lẹ́sẹ̀. Àwọn Métàlélọ́gbọ̀n náà ti ọwọ́ sìnkún Àjọ…

Eré Ìdárayá Ati Tẹtẹ Títa: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ṣèlérí Ìpèsè Àyíká To Rọrùn Fún Eré Ìdárayá Àti…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣèlérí láti pèsè ayika to rọrùn fún eré ìdárayá àti tẹ́tẹ́ títa fún àwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ náà àti gbogbo àwọn tí ọ̀rọ̀ náà kàn. Ẹni tíì ṣe Akọ̀wé Ìjọba, Ọ̀jọ̀gbọ́n Olanike Adeyemo ló sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí níbi ètò…

Èsì Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kano: Moni Ìgbàgbọ́ Pé Ilé Ẹjọ́ Tó Gajù Lọ Yóò Ṣe Ìdájọ́ Òdodo –…

Ẹni tíì ṣe èèkàn nínú ẹgbẹ́ òṣèlú New Nigeria People's Party (NNPP), Olufemi Ajadi Oguntoyinbo ti fi ọwọ́ sọ̀yà pé ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ (Supreme Court) yóò ṣe ìdájọ òdodo lórí Gomina Ìpínlẹ̀ Kano, Abba Yusuf. Oguntoyinbo tó jẹ́ bàbá…

Àsọdùn ọ̀rọ̀ ni ohun tí àwọn ènìyàn ń sọ nípa iye owó tí ìjọba àpapọ̀ fẹ́ fi ra ọkọ̀…

Asofin to n soju fun ẹkun Irẹpọ,Orelope  ati Ọlọrunsogo ní ipinlẹ Ọyọ, ọmọọba Lateef Ọlaide Mohammed ti ni ko si otitọ nipa ọrọ ti awọn eniyan ń sọ nipa iye owó ti ijọba apapọ fẹ fi ra ọkọ ti awọn asofin fẹ fi maa ṣe isẹ wọn. wọn…
button