Take a fresh look at your lifestyle.

Ìdókòwò Alábọ́dé Ni Ọ̀pákùtẹ̀lẹ̀ Ọrọ̀ Ajé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà – Mínísítà Jumokẹ Oduwọle

96

Mínísítà Fún Ilé Iṣẹ́, Òwò àti Ìdókòwò ti sàfirinlẹ̀ ipa tí ìsòwò alábọ́dé ńkó gẹ́gẹ́ bí ọ̀pákùtẹ̀lẹ̀ èyí tí ó ń mú ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà

 

Nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀ níbi ìfilọ́lẹ̀ ètò ìdókòwò ti ọdún 2025, èyí tí ó wáyé ní Ọjọ́bọ̀ ní ìlú Makurdi. Ọ̀mọ̀wé Oduwọle sàlàyé ipa tí ìsòwò alábọ́dé ń kó nínú ìdàgbàsókè ọrọ̀ ajé, ó wá pàrọwà sí ọmọ Nàìjíríà láti farajì fún ìdàgbàsókè ètò ọrọ̀ ajé

 

Ó tẹ̀síwájú pẹ̀lú títẹ́ pẹpẹ òfin àti àlàkalẹ̀ ìjọba èyí tí yóò mú ìlọsíwájú bá ìdókòwò alábọ́dé àti àwọn ètò tí yóò mú ìrọ̀rùn bá ìkópa nínú òwò síṣe

 

Comments are closed.

button