Take a fresh look at your lifestyle.

Ọmọ Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Pín Ẹ̀bùn Owó, Asọ Àti Àwọn Ohun Èlò Míràn Ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi

172

Ọmọ Asòfin tí ó ń sojú ẹkùn Ebonyi/Ohaukwu ní Ilé Asòfin Abuja, Pastor Eze Nwachukwu Eze ti fi àpò ìresì, Asọ, Ajílẹ̀ ta àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ́rẹ láti se ìrànlọ́wọ́ fún wọn síwájú ọdún kérésìmesì àti ọdún tuntun

 

Ó pín ohun èlò náà fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC àti àwọn tí ó kù díẹ kààtó fún láwùjọ

 

Ètò náà wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ Ebonyi, Ughodo

 

Nwachukwu salaye ìgbésẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí èyí tí ó wáyé láti fi ran àwọn eniyan rẹ lọwọ siwaju ayajọ keresimesi

 

Comments are closed.

button