Orílẹ̀-èdè Benin se ayẹyẹ òmìnira ọdún mẹ́tàlélọ́gọ́ta pẹ̀lú ààbò tí ó péye àti yíyan àwọn ọmọ ológun
Ààrẹ Tinubu ni àlejò pàtàkì níbi ayẹyẹ náà.
Àwọn gómìnà márùn-ún láti orilẹ-ede Naijiria ni o peju sibi ayẹyẹ naa
Lara wọn ni: Abdulrahaman Abdulrazaq ti ipinlẹ Kwara, Babajide Sanwo-Olu ti ipinlẹ Eko, Seyi Makinde, Oyo, Dapo Abiodun Ogun, ati Mohammed Bago ti ipinlẹ Niger .
Leave a Reply