Take a fresh look at your lifestyle.

Idris Elba Pé Fún Àlàáfíà Ní Orílẹ̀-èdè Sierra Leone

Ọlálékan Ọ̀rẹ́núgà

0 287

Òṣèré orí ìtagé orílẹ̀-èdè gẹ̀ẹ́sì Idris Elba, tó tún jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Sierra Leone tí pé fún àlàáfíà lẹyìn ìdìbò gbogbogbò ní Sierra Leone, èyítí o wáyé ní Ọjọ́ Àbámẹ́ta.

O rán àwọn ọdọ létí pé ọwọ́ wọ́n ní “àgbàrá” inú ìbò yìí wà, àti pé tí wàhálà bá ṣẹ̀lẹ̀ ní Orílẹ̀-èdè náà, kòní rọrùn láti tó pàdà.

Kìí ṣé àgbáyé nìkàn ló ń wò wa,” ṣùgbọ́n gbogbo Áfíríkà.

Ìdìbò ọjọ́ Àbámẹ́ta jẹ́ ẹ̀lẹ̀ẹ́kẹ́fa ní orílẹ̀-èdè náà lẹyìn ìgbà tí àwọn ológun tí gbá ìjọba ní ọdún 1992.

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button