Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Buhari Ṣẹ ọ̀fọ̀ Ọ̀gá ọlọ́pàá tẹ́lẹ̀ rí Tafa Balogun tó dolóògbé

0 240

Ààrẹ Muhammadu Buhari ti kí àwọn ẹbí, àwọn ọ̀rẹ́ àti àwọn alábàákẹ́gbẹ́ rẹ̀ bí ó ti ń kẹ́dùn ikú Inspector-General of Police (IGP), Mustapha Balogun.

Ó tún bá àwọn ọlọpa Orílẹ̀-èdè Nàíjíríà kẹ́dùn, nitori ibi ti olóògbé ti lo àkókò ti o dára jùlọ nínú ìgbésí ayé rẹ̀ nìyẹn.

Ó gbàdúrà fún ìsinmi àlááfíà fụ́n ọkàn olóògbé.

 

Ọláyinká Akíntọ́lá.

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button