Ààrẹ Nàìjíríà Ṣàfihàn Ìbànújẹ́ Rẹ̀ Lórí Ìkọlù Apànìláyá Tó Ṣẹ̀lẹ̀ Láìpẹ́ Yíì
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí kẹ́dùn lórí ìpàdánù ẹ̀mí méjì tí àwọn òṣìṣẹ́ ilé-iṣẹ́ ilẹ̀ America àti ọlọ́pàá Nàìjíríà méjì tí wọ́n tẹ̀lé wọ́n níbí ikọlù tí àwọn agbebọn kàn ṣé ní ìjọba ìbílẹ̀ Ogbaru ní Ìpínlẹ̀ Anambra.
“Inú mi bà jẹ́ gan-an…