Nàìjíríà, Palestine fìdí àjọṣepọ̀ wọn múl̀ẹ
Mínísítà Nàìjíríà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè, Aṣojú Yusuf Tuggar àti Aṣojú orílẹ̀-èdè Palestine sí Nàìjíríà, Muhannad Halmouri, ti gbà láti fì̀dí́ àjọṣepọ̀ ati ìfọwọ́wẹwọ́ aṣojú múl̀ẹ̀ láàrin orílẹ̀-èdè…