Àhesọ Lásán Ní Ìròyìn Ìdáwó Padà Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ – NELFUND
Àjọ Àkànṣe Ètò Ìyáwó Ẹ̀kọ́ Nàìjíríà (NELFUND) tí kọ àwọn ìròyìn tó ń pàṣẹ fún àwọn olùgbádùn owó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìjọba àpapọ̀ láti bẹ̀rẹ̀ sí san padà.
Olùdarí Ìbánisọ̀rọ̀ ti owó náà, Arábìnrin Oseyemi Oluwatuyi nínú ìkéde kan sọ pé àjọ…