Ìjọba Nàìjíríà Tún Ṣé Ìdánilójú Ìbọwọ̀ Sí Àdéhùn Wọ́n Pẹ̀lú Ẹ̀gbẹ́ Òṣìṣẹ́
Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní ọjọ́ Ẹtì tí fí dá àwọn ẹ̀gbẹ́ òṣìṣẹ́ lójú látí bọ̀wọ̀ fún àdéhùn tí wọ́n fọwọ́sí pẹ̀lú ẹ̀gbẹ́ òṣìṣẹ́ (NLC/TUC).
Gẹ́gẹ́bí Mínísítà tí Ìpínlẹ̀ fún Iṣẹ́, Ìyááfín Nkeiruka Onyejeocha, ìjọba kó ní ìrẹ̀wẹ̀sì nínú…