Ìrànlọ́wọ́ ọmọnìyàn jẹ wá lógún
Ìjọba Nàìjíríà ti sọ pé òun ti ṣetán láti tẹramọ́ akitiyan lórí ìdìdese àánú ọmọniyan jákèjádò orílẹ̀-èdè.
Eleyii waye bi Naijiria se darapọ mọ agbegbe lagbaaye lati ṣajọyọ ayajọ inu rere.
Nibi irin loju…