Ìpàdé Ẹgbẹ́ ECOWAS Tí Nlọ́ Lọwọ́
Ìpàdé tí ẹgbẹ́ àwọn Olórí Orílẹ̀-èdè tí Ìwọ̀-oòrùn Áfíríkà ECOWAS, tí fẹ́ bẹ̀rẹ báyìí ní Ilé-iṣẹ́ Ààrẹ, Abuja, Olú-ìlú Nàìjíríà.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Bola Tinubu, tó jẹ́ Alága ẹgbẹ́ náà ní yóò dárí ìpàdé náà.
Alága ECOWAS,…